Nuacht

Ìjọba Nàìjíríà ní àwọn máa lo owó náà láti fi ṣe àwọn ètò ìdàgbàsókè ní ẹ̀ka ìlera, ètò ẹ̀kọ́, ààbò àti àyíká.
Ní ọjọ́ kìíní oṣù Kẹta, wọ́n kéde Bola Ahmed Tinubu gẹ́gẹ́ bí ẹni tó gbégbá orókè níbi ètò ìdìbò ààrẹ tó tí ọ̀pọ̀ gbà pé òhun ló fẹ́ ẹ̀ ...