Nuacht

Ìjọba Nàìjíríà ní àwọn máa lo owó náà láti fi ṣe àwọn ètò ìdàgbàsókè ní ẹ̀ka ìlera, ètò ẹ̀kọ́, ààbò àti àyíká.
Ní ilé ààrẹ Aso Rock tó wà ní ìlú Abuja ni ààrẹ ti gbàlejò àwọn agbábọ́ọ̀lù náà lẹ́yìn tí wọ́n padà sí Nàìjíríà láti Morocco tí ìdíje náà ti wáyé.